yo_eph_text_reg/05/31.txt

1 line
511 B
Plaintext

\v 31 "Nítorí ìdí èyí ọkùnrin yóò fi Baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò sì darapọ̀ mọ́ ìyàwó rẹ̀, àwọn méjèjì yóò sì di ara kan." \v 32 Òtítọ́ tí ó pamọ́ yìí (jẹ́ èyí tí ó) ga - sùgbọ́n èmi ń sọ nípa Krístì àti ìjọ. \v 33 Síbẹ̀síbẹ̀, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín pẹ̀lú gbọ́dọ̀ fẹ́ràn ìyàwó rẹ̀, gẹ́gẹ́bí ara òun tìkárarẹ̀, àti wípé ìyàwó náà gbọ́dọ̀ bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀.