adesinaabegunde_yo_mrk_text.../04/10.txt

1 line
608 B
Plaintext

\v 10 Nígbà tí ó ku Jésù nìkan, àwọn tì ó sú mọ́ ọ àti ọmọ-ẹ̀yìn méjìlá bi í léèrè ìtumọ̀ òwe. \v 11 Ó sì dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin ni a fi adìtú ìjọba Ọlọ́run. Ṣùgbọ́n gbọgbọ rẹ̀ jẹ́ ówẹ́ fún àwọn tí ó wà ní ta, \v 12 wìpé bí wọ́n bá wò, bẹ́ẹ̀ni wọ́n wò, ṣùgbọ́n wọn kò ríran, Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé wọ́n gbọ́, bẹ́ẹ̀ni wọn gbọ́, kì yóò yé wọn, dípò bẹ́ẹ̀ ni wọn yóò sì yípadà, Ọlọ́run yíò sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì wọ́n!’ ”