adesinaabegunde_yo_2pe_text.../03/17.txt

1 line
414 B
Plaintext

\v 17 Nítorínà, ará, níwọ̀n tí ẹmọ àwọn ǹkan wọ̀nyí, ẹ pa ara yín mọ́ kí ẹ má ba lè sọnù pẹ̀lú ẹ̀tàn àwọn ènìyàn aláípòfinmọ́ kí o sìi pàdánù òtítọ́ rẹ. \v 18 Ṣùgbọń ẹ dàgbà nínu ore-ọ̀fẹ́ àti ìmọ̀ Ọlúwa àti Olùgbàlà wa Jésù Krístì. Kí ògo kó jẹ́ tí Rẹ̀ nísinsìnyí àti títí láíláí. Àmín