adesinaabegunde_yo_2pe_text.../01/10.txt

1 line
306 B
Plaintext

\v 10 Nítorínà, ará, sá ipáàrẹ láti jẹ́ kí ìpè àti yíyàn rẹ dá ọ lójú. Bí o bá ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyín, o kò ní subú. \v 11 Ní ọ̀nà yí wíwọlé sí ìjọba ayérayé ti Olúwa àti Olùgbàlà wa Jésù Krístì ní a ó fifún yín lọ́pọ̀lọpọ̀.