\v 1 Símónì Pétérù, ẹrú àti àpóstélì Jésù Krístì, sí àwọn tọ́ ti gba ìgbàgbọ́ iyebíye tí àwa náà ti gbà, ìgbàgbọ nínú òdodo Ọlórun àti Olùgbàlà wá Jésù Krístì \v 2 Kí Oreọ̀fẹ́ àti àláfíà máa pọ̀ si ní ìwọ̀n ọgbọ́n Ọlórun àti ti Jésù Olúwa wá.